Videos e Fotos Festival Ifá 2019

Festival de Ifá foi um sucesso, contamos com a presença do Oba (Rei) Aare Ogboni Igba Iwase Agbaye,de Ilé Ife, Nigeria, Baba Elegun de Nigeria. Devotos e filhos de Ifá do Brasil todo.

 

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

CATEGORIAS

Kábíyèsí Oba Adekunlé Aderonmu
Oba Ògbóni Iwashe

Presidente do Centro Cultural Africano, Nigeriano,
nascido em Abeokutá.

Olódùmarè, mo ji loni. Mo wo'gun merin aye.
Igun'kini, igun'keji, igun'keta, igun'kerin Olojo oni.
Gbogbo ire gbaa tioba wa nile aye.
Wa fun mi ni temi. T'aya-t'omo t'egbe - t'ogba, wa fi yiye wa. Ki o f'ona han wa. Wa f'eni - eleni se temi.
Alaye o alaye o. Afuyegegege meseegbe.
Alujonu eniyan ti nf'owo ko le.
A ni kosi igi Méjì ninu igbo bi obi.
Eyiti o ba ya'ko a ya abidun-dun-dun-dun.
Alaye o, alaye o.
Àse.